Add parallel Print Page Options

42 Ọlọ́run sì padà, ó fi wọn sílẹ̀ láti máa sin ogun ọ̀run: òòrùn, òṣùpá àti ìràwọ̀. Èyí wà ní ìbámu pẹ̀lú bí a ti kọ ọ́ nínú ìwé àwọn wòlíì pé:

“ ‘Ẹ̀yin ha mú ẹran tí a pa àti ẹbọ wa fún mi
    ní ogójì ọdún ní ijù bí, ìwọ ilé Israẹli?
43 Ẹ̀yin sì tẹ́wọ́gbà àgọ́ Moleki,
    àti ìràwọ̀ Refani òrìṣà yín,
    àwòrán tí ẹ̀yin ṣe láti máa bọ wọ́n.
Nítorí náà èmi yóò kó yín lọ sí ìgbèkùn rékọjá Babeli.’

Read full chapter

42 But God turned away from them(A) and gave them over to the worship of the sun, moon and stars.(B) This agrees with what is written in the book of the prophets:

“‘Did you bring me sacrifices and offerings
    forty years in the wilderness, people of Israel?
43 You have taken up the tabernacle of Molek
    and the star of your god Rephan,
    the idols you made to worship.
Therefore I will send you into exile’[a](C) beyond Babylon.

Read full chapter

Footnotes

  1. Acts 7:43 Amos 5:25-27 (see Septuagint)